Orin Ode
From Wikipedia
Orin Ode fun Aseye
Adeboye Babalola
Babalola
Adébóyè Babalolá (1973), Orin Ode fún Àseye. Ìlúpéjú, Nigeria: Macmillan Nigeria Publishers Ltd. Ojú-ìwé 216.
Orísirísi ìjálá ni ó wà nínú ìwé yìí. Díè nínú won ni àsè ìyò ára, òkú-síse, ilé-sísí àti béè béè lo. Orísìí ìjálá àti orin báwònyí tí ó wà nínú ìwé yìí jé mókànlá. Ìwé yìí tún se èkúnréré àlàyé nípa àwon òrò tí ó ta kókó