Lere Adeyemi
From Wikipedia
Bòsún Omo Òdòfin
Adébísí Johnson
Ebí
Lére Adéyemí (1997), ‘Yorùbá family Life as a Theme in Woman Narrative: A Feminist Approach’, Research in Yoruba Language and Literature 9 (Burbank (www.researchinyoruba.com)), ojú-ìwé = 86-89. ISSN-4322.
Òrò nípa ebí ni ó je ìwé yìí lógún. Bí òrò ebí se hàn nínú ìwé ìtàn-àròso ni ó mú gbó. Ìwé ìtàn-àròso tí ònkòwé lò ni ìwé ìtàn-àròso kan tí obìnrin kan tí orúko rè ń jé Adébísí Johnson ko. Orúko ìwé náà ni Bòsún Omo Òdòfin.