Iwe Ede Yoruba Apa Kiini

From Wikipedia

Iwe Ede Yoruba Apa Kiini

Adeboye Babalola

Babalola

Adébóyè Babalolá (1962), Ìwé Èdè Yorùbá: Apá Kínní: Ìkejà, Nigeria: Longman Nigeria Ltd. ISBN: O 63816 x. Ojú-ìwé – 139.

Àwon akékòó ní ilé-èkó gíga ni ìwé yìí wà fún. Àwon akékòó olódún kìíní àti olófún kejì ni apá kìíní yìí wà fún. Lésìnnì kan ni ó wà fún òsè kan. Ogún ìtàn ni ó wà nínú rè. Léyìn ìgbà ti omo bá ka ìtàn kòòkan tán ni yóò wá sisé lórí àwon nnkan bíi àgbékà Yorùbá, àsìko àti àsìso Yorùbá, Gírámà Yorùbá àti àròko. Òpòlopò àwòrán ni ó wà nínú ìwé náà láti lè jé kí ohun tí ònkòwé ń so yé ònkàwé.