Omo Oku Orun
From Wikipedia
Omo Oku Orun
J.F. Odunjo
Odunjo
J.F. Odúnjo (1964), Omo Òkú Òrun. Lagos, Nigeria: African Universities Press. Ojú-ìwé 52.
Orí wálé ti gbogbo ènìyàn ń pè ní omo òkú òrun ni ìwé yìí dá lé. Gbogbo ìyà tí wálé je láti owó Àbèké, ìyàwó baba rè, ni ìwé yìí ménu bà. Ìwé yìí kò sàìménu ba bí eni tí a pè ní òkú òrun tún se di alààyè. Ìwé yìí ní àtúnyèwò èkó tí ó kún fún ìbéèrè tí ó lè jé kí ohun tí àwon ònkàwé kà yé won.