Smith, Robert
From Wikipedia
J. Adé Àjàyí and Robert Smith (1971), Yoruba Warfare in the 19th Century. Ibadan, Nigeria: Ibadan University Press in association with the Institute of African Studies, University of Ibadan and the Cambridge University Press. Ojú-ìwé 172.
Orí àwon ogun tí ó wáyé ní séńtúrì kokàndín lógún ni ìwé yìí dá lé. Apá méjì ni ìwé yìí pín sí. Robert Smith ni ó ko apá kìíní tí ó sòrò lórí orísirísI agun tí ó wáyé ní ilè Yorùbá láàrin 1820 sí 1893. J. Adé Àjàyí ni ó ko apá kejì. Níbè, ó sòrò lórí ogun ìjàyè. Àfikún méjì ni ìwé náà ní. Àfikún àkókó sòrò nípa ohun tí ògágun jone so nípa ogun Ègbá. Àfikún kejì sòrò nípa ogun òsà (Lagoon warfare). Òpòlopò máàpù àti àwon ìwé ìtókasí ni ìwé náà ní.