Ajayi, Sir Olaniwun
From Wikipedia
Sir Olaniwun Ajayi (2005), This House of Oduduwa must no fall. Ibadan, Nigeria: Y-Books. ISBN: 978-2659-37-1. Ojú-ìwé 351
Òrò nípa orílè-èdè Nàìjíríà ni ìwé yìí dá lé sùgbón tí Sir Àjàyí fi ojú omo Yorùbá ko. Ojú omo Yorùbá ni ó fi wo bí orílè-èdè Nàìjíríà se rí lóni. Ó bèrè láti orí ìgbà tí àwon Gèésì ti ń se ìjoba lé wa lóri dé orí wàlálà òsèlú tí a ní ní ilè Nììjíríà títí di odun 2005. Ìwé tí ó ye kí gbogbo omo Yorùbá kà ni