Yoruba Literature
From Wikipedia
Litireso Yoruba
Yoruba Literature
Molomo Babajamu
Babajamu
Malomó Babajamu (1959), Yorubá Literature. Ilorin: Nigerian Publications Service. Ojú-ìwé 306.
Lékè pé Lítírésò Yorùbá ni orúko ìwé yìí, ó sòrò nípa gírámà àti àsà Yorùbá náà. Àwon oníwèé méwàá àti àwon tí ó ń lo sí ilé ìkósé olùkóni ni ìwé náà wà fún. Àwon ohun tí ó wà nínú sílábóòsì Yorùbá ni ìwé yìí kókó ménu bà ó sì sòrò nípa won ní òkòòkan.