This House of Oduduwa Must Not Fall
From Wikipedia
Ile Oduduwa
This House of Oduduwa Must Not Fall
Sir Olaniwun Ajayi
Olaniwun
Sir Olaniwun Ajayi (2005), This House of Oduduwa must not fall. Ibadan, Nigeria: Y-Books. ISBN: 978-2659-37-1. Ojú-ìwé 351
Òrò nípa orílè-èdè Nàìjíríà ni ìwé yìí dá lé sùgbón tí Sir Àjàyí fi ojú omo Yorùbá ko. Ojú omo Yorùbá ni ó fi wo bí orílè-èdè Nàìjíríà se rí lóni. Ó bèrè láti orí ìgbà tí àwon Gèésì ti ń se ìjoba lé wa lóri dé orí wàlálà òsèlú tí a ní ní ilè Nììjíríà títí di odun 2005. Ìwé tí ó ye kí gbogbo omo Yorùbá kà ni.