Looya Omo Yoruba
From Wikipedia
Awon Agbejoro Omo Yoruba
Àwon Lóóyà àkókó ní ilè Nàìjíríà tí wón jé omo Yorùbá. A ko odún tí wón sí òkè orúko won
1880 Christopher Alexander Sapará Williams Òun ni omo Nàìjíríà tí ó kókó di Lóóyà
1892
Rotimi Olusomoha Aládé
1900
John Augustus Otunba Payne
1905
E.J. Alexander Taylor
1909
John Akinola Òtúnba Payne
1910
Sir Adéyemo Alákijà 1913 Oláyímíká Alákijà
Ithiel K Ladipo Doherty
Olaseeni Moore 1921 E. A Franklin
Alfred Latunde Johnson
E.M.E. Àgbètì
T.A. Dolierty
1922
Adédépò Káyòdé
S.H.A. Baptist.
1923
Ayòdélé Williams
Steven Bánkólé Rhodes
A.O.D. Dòsùnmú
Adébíyí Désàlú
1924
C.A. Harrison Obáfémi
Muhammed Lawal Basil Agusto
A. O. Àbáyòmí
I.O. Caxton Martins
Rufus Adékúnlé Wright
Adégúnlè Sóètán
1925
F.O. Lucas
A. O. Thomas
Albert Horatus Akíntúndé Doherty
1926
J. Omoliyì Coker
Isaac Kúshìkà Roberts
F. Tátúndé Vincent
John Martins
1927
T. Ekúndayò Kusimo Sórìnólá
Akínbónà Sólúadé
1928
Samuel Ayòdélé Thomas
Frances Edney Euba
1929
Omósànyà Adéfólú
Richard Adé-Èyò Doherty
Hezekiah Ajayi Johnson (Alias Onibuwe)
Àlàbá Akéréle
1930
Abíólá Akínwùmí
1931
Ògúnyemí Ebíkúnlé Ajósè
1933
Olúwolé Ayòdélé Alákijà
1934
Adébíyí Májékódùnmí
1935
Olájídé Oláríbigbé Alákijà
1936
Akinolá Adésògbìn
1940
Adélékè Adédoyin
Ladipo Odúnsì
1941
Oladipo Moore
John Idowu Conred Taylor
1942
Christian Adéségun Wilson
Odúnbákú
Olátúndé Balógun
Bòdé Thomas
1944
Àlàbí Taylor
1946
John Adéjùmò Kester
funso Blaize
Akíntóyè Téjúosó
Obájénu Awólówò
1947
H.O. Davies
Olájídé Sómólú
S.A. Adéoba
Victor Ìlòrí
C.O. Awóyelé
S. Àyìnlá Abina
Rèmí Fàní-Káyòdé
T.O.S. Benson
L.O. Fádípè
V.A. Déhìmò
G.B.A. Coker
E.A. Caxton-Martins
1948
M.O. Oyàmádé
J.O. Kassim
O.A. Akántóyè
A.O. Lawson
Dúró Phillips
Àtàndá Fàtáì-Williams
O. Akínkúgbé
Abíódún Akéréle
Ayò Rósìji
M.A. Adésànyà
V.O. Èsan
Basheer Agusto
1949
C.O. Madarikan
A.O. Lápité
D.O. A. Ògúntóyè
G.S. Sówèmímò
J.O. Beckley
1950
Adé Mummey
S.O. Lámbò
Adégbóyèga Adémólá
J.A. Adéfarasìn
S.L. Akíntólá
L.J. Dòsùmú
Isin Shotire
D.M.O. Akínbíyi
C.O. Ògúnbánjo
A. Òkúbádéjo.
Ayò Òkúsàga
Oláyínká Olámosu
O.O. Omololú
H.M. Àllí-Balógun
A.M.A. Akinloyè
1952
A.G.O. Agbájé
Akinolá Àgùdù
J.O. Ajíbólá
B. Olówófóyèkù
E.B. Craig
E.O. Ayòolá
1953
O. Ajósè-Adéògún
S.A Ògúnkéye
D.O. Coker
Adéníran Ògúnsànyà
S.L. Dúrósaró
A.R. Bákàrè
S.B. Adéwùnmí
Adénékàn Adémólá
S.D. Adébíyí
Adédàpò Adérèmí
A. E. Molajo
O. Òráfidíyà
Ayò Richards
Àdùké Moore
E.O. Fákáyòdé
G.B.A. Akínyedé
Andrew Ajíbólá
1954
O.B. Akin Olúgbadé
A.F.O. Dábírí
S.A. Awólèsì
A. Adésidà
Kéhìndé Sófolá
Adédòkun Hastrup
J.A. Odékù
Búsàrí Òbísèsan
O.A. Fájémisìn
D.O. Ògúndìran
Káyòdé Èsó
Y.A. Jìnádù
S.O. Abudu
1959
B.O. Babalákin
Y.O. Àdìó
Oláyínká Ayòolá
Àbáyòmí Olówòfóyèkù
Lóyà àkókó ní ilè Nàìjíríà tí ó jé omo Nàìjíríà ni Williams Alexander Sapara Williams. Ó di agbejórò ní odún 1880. Omo Yorùbá nì Májísíréètì kìíní ní ilè Nàìjíríà tí ó jé omo Nàìjíríà ni Sir Olumuyiwa Jibalaru. Odún 1938 ni ó di Majísíréètì yìí. Òun náà ni omo Nàìjíríà kìíní tí yoo di adájó ilé-ejó kóòtù gíga (High Court of Judge). Omo Yorùbá ni Omo Nàìjíríà àkókó tí yóò di ‘Chief Justice’ ilè Nàìjíríà ni Sir Adétòkunbò Adémólá. Omo Yorùbá ni Omo-oba Abéòkúta ni.
Lóyà tí ó kókó gba ‘Senior Advocate of Nàìjíríà ‘Chief F.R.A. Williams. Omo Yorùbá ni.
Lóyà obìnbìn àkókó tí ó jé omo Nàìjíríà tí yóò di adájó ilé ejó àgbà (High Court Judge) ní ilè Nàìjíríà ni Mrs Modupe Omo-Eboh tí ó jé omo Akingbehin. Omo Yorùbá ni.
Òbìnrin Nàìjíríà tí yóò gba oyè Senior Advocate of Nigeria’ nimo o tí ó jékóàkó Yorùbá nìmo. OolankeMrs Folake S
‘Attorney-General’ ti tí yóò jekó Nàìjíríà àkómo‘O Nàìjíríàilè ni Dr di ‘President ofkó Aáfíríkà tí yóò kó ilèmolawale Elias Òun ni oTeshim O Yorùbá nimothe International Court of Justices’. O di ‘Knight’ ni sokón yóò kó Nàìjíríà tí womoyà oLó Yorùbá nimoSir Kitoyi Ajasa. O