Iwe Ede Yoruba Apa Kinnii
From Wikipedia
Iwe ede Yoruba Apa Kinni
Adeboye Babalola
Babalola
Adébóyè Babalolá (1962), Ìwé Èdè Yorùbá: Apá Kínní: Ìkejà, Nigeria: Longman Nigeria Ltd. ISBN: O 63816 x. Ojú-ìwé – 139.
Àwon akékòó ní ilé-èkó gíga ni ìwé yìí wà fún. Àwon akékòó olódún kìíní àti olófún kejì ni apá kìíní yìí wà fún. Lésìnnì kan ni ó wà fún òsè kan. Ogún ìtàn ni ó wà nínú rè. Léyìn ìgbà ti omo bá ka ìtàn kòòkan tán ni yóò wá sisé lórí àwon nnkan bíi àgbékà Yorùbá, àsìko àti àsìso Yorùbá, Gírámà Yorùbá àti àròko. Òpòlopò àwòrán ni ó wà nínú ìwé náà láti lè jé kí ohun tí ònkòwé ń so yé ònkàwé.