Research in Yoruba Language and Literature 9
From Wikipedia
Jona Akada Ede Yoruba Nonba 9
Research in Yoruba Language and Literature 9. Burbank: Technicians of the Sacred. ISSN: 1115-4322. Website: www.researchinyoruba.com
Nínú nóńbà yìí, àwon ònkòwé mérìnlá ni ó ko átíkù sínú rè.
A. Adégbìté tí ó wà ní Dept of Music, OAU, Ife, Nigeria ko nnkan lórí tìlùtìfon. Ó pe átíkù rè ní ‘The Effect of Acculturation on the Contemporary Popular Music”,
Bòdé Agbájé tí òun náà wà ní Dept of African Languages and Literatures, OAU, Ife Nigeria ko nnkan lé orí ‘A Socio-Historical Appraisal the Yoruba Orature”,
Bádè Àjàyí (Dept of Linguistics and Nigeria Languages, University of Ìlórin Nigeria ko nnkan lórí Ifá tí àkolé rè jé ‘The Language and Style of Ifa Literary Corpus”,
Javier Perez de Cuellar ko nnkan lé orí ‘A Marshall Plan for Culture and Development Culture’,
O. Olúránkinsé (Adéyemí College of Education, Ondó, Nigeria) ko nnkan lórí ìmúnimòtélè. Ó pe àkolé isé rè ní ‘Element of Prognosis Kólá Akínlàdé’s Yorùbá Novels’,.
P.S.O. Àrèmú àti T.Y. Ògúnsiakin (Dept of Fine Arts, OAU, Ifè, Nigeria) ko nnkan lé orí ‘Red, Black and White Inevitable Currencies in Yorùbá Traditional Religion”, #
‘African-American Spirituals; A Study of Bi-cultural Influence ni àkòrí ohun tí O. Oláníyan (Dept of Music, OAU, Ifè, Nigeria) ko nnkan lé lórí.
O.O. Bátèye (Dept of Music, OAU, Ifè, Nigeria) ko nnkan lérí ‘Mood Setting/Pictorial Imagery in the Nigerian Art Song’,
B.O. Oláyinká (Dept of Religious Studies, OAU, Ifè, Nigeria) ko nnkan lérí òwe. Ó pe isé rè ní ‘Proverbs: Issues of Yoruba Femininity from a feminist Hermeneutical Perspective’.
O. Adébòwálé (Dept of Languages and Liguistics, Adékúnlé Ajásin University, Àkùngbá-Àkókó, pe àkòrí isé rè ní ‘Political Communication in Yorùbá Novels’.
Èka-èdè Ìjèsà ni Kinyò Bólórundúró (Òsun State College of Education, Ilésà, Nigeria) ko nnkan lé lórí. Ó pe àkòrí isé rè ní ‘The “Language” of the Ìjèsà’.
O. Oyèsakin (Dept of Yorùbá and Communication Arts, Lagos State University, Lagos, Nigeria) ko nnkan lórí ewì ìbílè. Ó pe àkolé isé náà ní ‘Performance in Yoruba Poetry Revisited’.
Lérè Adéyemí (Dept of Linguistics and Nigerian Languages, University of Ìlórin, Nigeria) ko nnkan lórí àwon obìnrin. Ó pe àkòrí isé rè ní ‘Yoruba Family Life as a Theme in Wester narratives: A Feminist Approach’.
Solá Owóníbi (Ládòkè Akíntólá University of Technology, Ògbómòsó, Nigeria) ko nnkan lérí àwon obìnrin nínú isé tí ó pe àkòrí rè ní ‘The Semantic of Women Oppression: A Linguistic Analysis’.
A lè wá pín àwon isé mérèèrìnlá yìí sí Tìlùtìfon, orin (Music) – A. Adégbìté O. Oláníyan ati O. O. Bátéye Lítírésò alohùn (Orature) - Bòdé Agbájé Culture (Àsà) – Javier Perez de Cueller, O. Oláníyan Novels (Ìwé ìtàn-àròso) – O. Olúránkinsé, O. Adébòwálé Prognosis (Ìmúnimòtélè) – O. Olúránkinsé Èsìn (Religion)- P.S.O. Àrèmú àti T.Y. Ogunsiakin Isé onà (Arts) – P.S.O. Àrèmú àti T.Y. Ogunsiakin Òrò nípa obìnrin (Femenism) – B.O. Oláyínká, Lérè Adéyemí, Solá Owóníbi Òwe (Proverb) – B.O. Olayinka Èka-èdè (Dialect) - Kínyò Bólórundúró Òsèlú (Politics) – O. Adébòwálé Ewì (Poetry) – O. Oyèsakìn Ebí (Family) – Lére Adéyemí Ìtumò (Semantics) - Solá Owóníbi