Ewì Ológundúdú

From Wikipedia

Ewi Oloogundudu

Ewi

Oloogundudu

A.S. Oyewale

Oyewale

Ajemo-oselu

Oselu

A. S. Oyewale (2003), ‘Ìtúpalè kókó-Òrò Ajemósèlú nínú Ewì Ológundúdú’., Àpilèko fún Oyè Eémeè, DALL, OAU, Ifè, Nigeria.

[edit] Àṣ amọ̀

Àgbéyèwò kókó-òrò ajemósèlú ilè Nàìjíríà gégé bí ó ti se jeyo nínú ewì Ológundúdú ni ó je isé yìí lógún. Àpilèko yìí se òfìntótó ìtàn nípa ìsèlú ilè. Nàìjíríà ní ìbámu pèlú ojú tí akéwì fì wo àwon òrò ìsèlú náà. Èyí wáyé léte àti gbé isé akéwì náà lérí ìwòn àti èròngbà láti mú kí ìwòye wa lè gbòòrò nípa ojú tí a fi ń wo òrò ìsèlú ìgbàlódé ní orílè-èdè Nàìjíríà gégé bí akéwì ti sàgbékalè rè. Fún àpilèko yìí ní pàtó, a se àsàyàn àwon ewì tí Ológundúdú ti ménuba òrò nípa ìsèlú Ìgbéléwòn isé náà dá lórí fífi tíórì ìfojú-èrò-Marx-wo-lítírésò gégé bí i tíórì àmúlò. Isé yìí se àkíyèsí nínú ewì Ológundúdú pé, àwon kókó-òrò tó je mó ìsèlú ilè Nàìjírí lóje akéwì náà lógún jùlo. Fún ìdí èyí, isé àpilèko yìí fihàn pé, àwon akéwì ìgbàlódé Yorùbá ti bèrè síi nawójà won kojá agbo Yorùbá títí dé orílè èdè Nàìjíríà lápapò. Bákan náà, isé ìwádìí yìí fìdí rè múlè pé àwon akéwì Yorùbá kì í se afonrere àwon ìsèlè nìkan sùgbón wón tún jé agbáterù fún àlààfíà àti ètò ìsèjoba tó móyán lórí. Agbéyèwò àwon kókó-òrò inú ewì Ologúndúdú fihàn pé, ohun tó je é lógún jùlo ni láti se ìkìlò fún gbogbo àwon tó ń kópa nínú ìsèlú ìgbàlódé ilè Nàìjíríà láti se pèlé. Ohun tó je é lógún la sàpèjúwe gégé bí i lámèyító tí ewu isé rè dá lórí ojúsàájú síse. Àkíyèsí wa nínú isé Ológundúdú ni wí pé, o máa ń se ojúsàájú, ìdájó àìkógo já, àti sísé àfihàn òduwòn àwon ènìyàn àti ìsèlè láìmímò kíkún nípa won.


Orúko Alábòjúútó: Òmówé A. Akínyemí

Ojú ìwé: 303