Ifojusun-Ajemodanwo

From Wikipedia

Ifojusun-Ajemodanwo

L.O. Adewole

W.O. Fatokun

M.O. Mabayoje

Ore Yusuf

Exam Focus: Yoruba

L.O. Adewole, W.O. Fatokun, M.O. Mabayoje and Ore Yusuf (200), Ìwé Ìfojúsùn Ajemó-Dánwò Èdè Yorùbá fún WASSCE, SSCE àti UME (Exam focus: Yoruba Language. Ibadan, Nigeria: University Press PLC. Ojú-Iwe 140. ISBN: 978 030692 7.

Òrò Àkóso

A ko Ìwé Ìfojúsìn Ajemó-Dánwò Èdè yorùbá yìí fún ìgbáradì ìdánwò àsekágbá ti ilé-èko sékóńdìrì àgbà. Nítorí ìdí èyí, gbogbo ohun tí ìlànà isé (Kòríkúlóòmù àti Sílábóòsì0 se àgbékalè rè fún ìdánwò yìí ni a ménu bà.

Yàtì sì èyí, gbogbo ohun tí ó se-kókó ni a tú palè ní orí-òrò, lábé èkó kòòkan. Ní òpin orí-òrò kòòkan, a bèèrè àwon ìbéèrè, a sì dáhùn won. Léyìn èyí ni a tún wá fún àwon asèdánwò ní òpòlopò ìbéèrè èwo-nì-dáhùn àti ìbéèrè agbàròko tí won lè fi dánrawò fún ìgbáradì.

A dúpé púpò lówó Àjo WÀÉÈKÌ àti JÁMBÙ fún gbígbà wá láàyè láti lo àwon ìbéèrè won tí wón ti se kojá. Kò sí tàbí-sùgbón nípa ti pé ìwé yìí yóò wúlò gidigidi, pàápàá fún àwon tí ó ń gbélé se yálà ìdánwò SSCE tàbí ti WASSCE.

ÌTÓKA ÀKÓÓNÚ

Èkó 1: Ìfáárà

Èkó 2: Àkàyé

Èkó 3: Àròko

Èkó 4: Létà Kíko

Èkó 5: Èyà Ara Ìfò àti Ipa

Èkó 6: Fóníìmù àti Fóònù

Èkó 7: Sílébù

Èkó 8: Jíjeyopò àti Ànkóò Fáwèlì

Èkó 9: Àrànmó

Èkó 10: Ìró Pípaje tàbí Ìpaje

Èkó 11: Òrò Àyálò

Èkó 12: Ohùn

Èkó 13: Àkotó

Èkó 14: Mófíìmù

Èkó 15: Ìhun Òrò: Ìsèdá Òrò-Òrúko tàbí Ìsodorúko

Èkó 16: Òrò-Orúko

Èkó 17: Òrò-Ìse

Èkó 18: Òrò-Àpónlé, Òrò-Atókùn àti Òrò-Àpèjúwe

Èkó 19: Òrò-Arópò-Orúko àti Òrò-Asopò

Èkó 20: Ìsòrí Gírámà

Èkó 21: Gbólóhùn

Èkó 22: Àpólà àti Awé-Gbólóhùn

Èkó 23: Aáyan Ògbufò

Èkó 24: Afò Asafò àti Afò Àgbàrán